a picture showing moyo okediji sitting next to his artwork

To all Omo a yọ orù bá wọn tọ́jú ọmọ tuntun

1. To all Omo a yọ orù bá wọn tọ́jú ọmọ tuntun;

Ọmọ́ gbó,

Orù ò gbó:

the offspring of those who bring out the orù pot of herbs to care for infants;

the baby prospers,

and the pot does not falter.”

Ọmọ a yọ orù bá wọn lówó lọ́wọ́. (Those who bring out the pots of wealth)

Ọmọ a yọ orù bá wọn bímọ lémọ (Those who own the pots of fertility)

Ọmọ a yọ orù bá wọn níre gbogbo. (Owners of the pots with immeasurable treasures).

Ọmọ a yọ orù bá wọn tún ohun gbogbo ṣe. (Those with a pot full of all that mend the world).

2.1 Olodumare says all is well with us.

That we are fine.

That our future is great.

That what we experience now, in this time of pain and struggles,

is just a test of our resolve—to make us stronger people,

with a vision and a will to fashion for ourselves

and our people a brilliant future,

hewn out of the challenges of the present, and knowledge of the past.

2.2 Olodumare is aware of our predicaments.

She reveals that she knows that the times are tough;

It is true that food is expensive;

that the cost of housing is high;

that the prices of the basic things that we need to survive in the world

are way beyond the reach of many of us:

but Olodumare says these are the signs that we need

to understand that we are at the point when things will turn for the better for us.

3. Olodumare says we are marathon runners: when we are near the finishing point is when things are the most difficult, when the runner is most tired, thirsty, weakest and almost ready to give up, to collapse, to fall down and fail.

4. Olodumare says we must keep hope alive.

We must not consider despair.

We must not think of gloom.

We must put aside all thoughts of doom.

Because our flower is about to bloom out of the barrenness of the rock on which we stand.

5. Olodumare, in Oyeku meji, says:

Ọ̀yẹ̀kú Méjì vision appeared for Omo a yọ orù bá wọn tọ́jú ọmọ tuntun, a people looking up to ọ̀run for their salvation.

The question posed for Ifa divination is this: “What does the future hold for us, as a people facing enormous struggles, when hope seems dims for us?” The following excerpt from the Ọ̀yẹ̀kú Méjì verse is what appeared in reference to this question:

10. Ọ̀pẹ̀lẹ̀ ló yó tán ló dakùn délẹ̀

A dífá fun Peregede

Tí ń ṣe yèyé Ojúmọ́mọ́

Ẹbọ ni wọ́n ní kó wá ṣe

Ó gbébọ níbẹ̀ ó rú

15. Ojúmọ́ tó mọ́ wa lénìí

Ojúmó ajé ni kó j̣ẹ́

Peregede, ìwọ ni yèyé ojúmọ́mọ́

Ojúmọ́ tó mọ́ wa lénìí

Ojúmọ́ ire gbogbo ni kó jẹ́

20. Peregede, ìwọ ni yèyé ojúmọ́mọ́

Translation :

Feeling well fed and satisfied, Òpèlè reclined on her belly

Casting Ifá for Peregede

The mother of the dawn

25. She was advised to offer sacrifices

She complied

This new dawn shall be a dawn of blessing

Peregede you are the mother of dawns

This new dawn shall bring all good things of life

30. Peregede you are the mother of dawns.

–Moyo Okediji, Austin, TX

**The photo shows Ilẹ̀, a wall mirror done with the soil.

In the soil of the land is revealed the truth of a people.

Interested in some of my published works?

Similar Posts

Leave a Reply